GBAJUMO

SAKA Ọ̀RỌ̀BỌ̀ ṢÈDÁRÒ ỌBA ONÍRÙ TÓ KÚ * Ó NÍ, AKỌNI ŃLÁ LÓ LỌ NÍ NIGERIA


Oba Oniru
Aare egbe àwn olorin fuji nígbà kan, Alhaji Saka Ayinde Odunsi ni tàwn èèyàn tún mo sì Saka Orobo tí àpèjúwe ba Oniru, Alayeluwa Oba Idowu Abiodun gege bí òpó ńlá kán to wo nílé Yoruba lójijì, táwn èèyàn kò ní í gbàgbé láéláé.
Orobo nínú ọ̀rọ̀ s pé, títí láyé ni iran Yoruba ati Nigeria lapapo yóò máa rántí ipa manigbagbe tí ba Oniru kò laarin m adarihunrun
Ó fi kún un pé ilosiwaju rere ti Kabiyesi náà mú bá ìlú e, Eti-Osa, ipinle Eko lapapo kò e fowo ro seyin rárá, bẹ́ẹ̀ ni àjọṣepo to dán moran to ni pẹ̀lú àwn ba alayé akgbẹ́ e ko sai mú eto àlàáfíà to dara wá ní gbogbo àgbègbè àtàwn íbi tó sún mọ́ n.
Lára àwn ohun iwuri tí Kabiyesi yìí e nígbà ayé ní eto ilé kiko lọ́nà ìgbàlódé sì Oniru estate ni Victoria Island, l"Ekoo èyí tó mú ìlú e rwà gidi, tó sì s ó di apewaawo lágbègbè ohun."
Saka Orobo, olorin fuji
Orobo nínú ọ̀rọ̀ s pé "Mo ń fi asiko yii sedaro pelu awon molebi ba Óniru, àwn aráàlú lori ikú Oba wá, Alayeluwa Oba Idowu Abiodun Oniru. Ikaya ńlá ni ikú ohun je sugbon a dúpẹ́ wí pé ismi tó dara ni wn lo, bẹẹ ni wn fi igbe ayé wn e òpòlopò èèyàn looore kí Olúwa bá wa ké wn, kò fi wn sì àlùjonna onidera.
“Nígbà ayé wn, bàbà dáadáa ní wón, tí ilé àti ona wn gba gbogbo èèyàn, ìdùnnú àti àlàáfíà ni ba Idowu Abiodun Oniru máa ń wà fún gbogbo ènìyàn, èyí tó mú un yàtò púpò, tí àwn èèyàn sì máa ń rí í gege bíi bába gbogbo ìlú "
Odun 1937, ní wón bí Oba Idowu Abiodun Oniru, jọ́ Aje Monde ose yìí ni Kabiyesi ohun jáde láyé léni dún mejilelogorin.


Post a Comment

0 Comments